Bàtà Magazine Logo
african-print-mask

Bàtá Magazine

Our first issue released in January, featuring five poems from four authors. Check it out here!

LATEST POEMS

Read our latest poems or browse the archives.

The Ancestral Dance Feast.

ÌGBÀ-Ǹ-BÁ JÓ, ONÍLÙ DÁGBÉRE AKÉ

Qudus Ọlánrewájú Òjíkùtù (Bàbá òwe)

Kòkòrò ni mí, n ò mọ ibi a kìí kọjú ijó sí. Gúdúgúdú ni mí, n ò mọ ibi a kìí fi ẹsẹ̀ ìlù sí Bí mo bá ń jó

The Great Aspiration

ORÚKỌ: ẸRÙ TÍ KÒ NÍ ÒṢÙKA

Qudus Ọlánrewájú Òjíkùtù (Bàbá òwe)

Kí ìyá mi tó bími Bàbá mi ti bí ìrètí Bàbá mi, Ìyá mi, pẹ̀lú ìrètí wọn ni wọ́n fi orúkọ fún mi bí a ti ń fún ọba ládé

From The Line of Great Elements

Ìṣọ̀làá

Tukur Ridwan

Mo tẹ̀síwájú pẹ̀lú yíyí afẹ́fẹ́, tí ń gbá erùpè Kúrò lójú ọ̀nà mi, láti ṣí ọ̀nà sí ìjọba àtijọ́ Ti àwọn baba ńlá mi. Mo wá láti bùkún

If They Can Pronounce Schwarzenegger.

Ìṣòro, bí wọ́n bá pè ọ ní Ayọ̀déle, àti pé ahọ́n wọn máa yọ̀ sórí fawelì bí okuta ìbòṣepọ̀. Ìṣòro, bí wọ́n bá dín án kù sí Ayọ̀

Baby and The Bee

Nígbà tí a bá bí omo wọ́n má kán oyin sẹ́nu rẹ̀, ṣùgbọ́n kò sí ẹni tó sọ fún un pé, ayé kì í dun títí, ati pé pípé jé ìrújú

african-print-mask

Anvil

Adedayo Agarau (Translation by Alfred Olaiya)

Kókósẹ | ninú àlá yẹn òún gbé ike omi láti ẹ̀yìnkùlé níbití ìyá wa ti gbé pè ó ní ohùn òkè ó sì sáré gba