
ÌGBÀ-Ǹ-BÁ JÓ, ONÍLÙ DÁGBÉRE AKÉ
Qudus Ọlánrewájú Òjíkùtù (Bàbá òwe)
Kòkòrò ni mí, n ò mọ ibi a kìí kọjú ijó sí. Gúdúgúdú ni mí, n ò mọ ibi a kìí fi ẹsẹ̀ ìlù sí Bí mo bá ń jó

Qudus Ọlánrewájú Òjíkùtù (Bàbá òwe)
Kòkòrò ni mí, n ò mọ ibi a kìí kọjú ijó sí. Gúdúgúdú ni mí, n ò mọ ibi a kìí fi ẹsẹ̀ ìlù sí Bí mo bá ń jó

Qudus Ọlánrewájú Òjíkùtù (Bàbá òwe)
Kí ìyá mi tó bími Bàbá mi ti bí ìrètí Bàbá mi, Ìyá mi, pẹ̀lú ìrètí wọn ni wọ́n fi orúkọ fún mi bí a ti ń fún ọba ládé

Tukur Ridwan
Mo tẹ̀síwájú pẹ̀lú yíyí afẹ́fẹ́, tí ń gbá erùpè Kúrò lójú ọ̀nà mi, láti ṣí ọ̀nà sí ìjọba àtijọ́ Ti àwọn baba ńlá mi. Mo wá láti bùkún

Ayomide Okeowo
Ìṣòro, bí wọ́n bá pè ọ ní Ayọ̀déle, àti pé ahọ́n wọn máa yọ̀ sórí fawelì bí okuta ìbòṣepọ̀. Ìṣòro, bí wọ́n bá dín án kù sí Ayọ̀

Titilayo Matiku
Nígbà tí a bá bí omo wọ́n má kán oyin sẹ́nu rẹ̀, ṣùgbọ́n kò sí ẹni tó sọ fún un pé, ayé kì í dun títí, ati pé pípé jé ìrújú

Adedayo Agarau (Translation by Alfred Olaiya)
Kókósẹ | ninú àlá yẹn òún gbé ike omi láti ẹ̀yìnkùlé níbití ìyá wa ti gbé pè ó ní ohùn òkè ó sì sáré gba

Abdulbaseet Yusuff (Translation by Adesiyan Oluwapelumi)
Wàhálà Púpọ̀ Nínú Orílẹ̀-Èdè Yìí | Wàhálà, bí o bá jẹ́ Olùwòran, tí o ń wo ìwọ́de láti òkèèrè pẹ̀lú ọwọ́ rẹ wà nínú àpò

Mayowa Oyewale (Translation by Adesiyan Oluwapelumi)
Kí lódé tó fi dáhùn ní èdè Yorùbá | Tí mo bá bá ọ sọ̀rọ̀ ní èdè Gẹ̀ẹ́sì/ bí àwọn Òyìnbó ṣe ń ṣe é/ pẹ̀lú ahọ́n tí ó nípọn